Fati Lami Abubakar tí wọ́n bí lọ́jọ́ Kejìlá oṣù kẹrin ọdún 1951 (12 April 1951) jẹ́ Adájọ́ àgbà Ìpínlẹ̀ Niger, Obìnrin àkọ́kọ́ fún Nàìjíríà àti Aya Ààrẹ-àná, Abdulsalami Abubakar lọ́dún 1998 sí 1999.
Ó di Adájọ́ àgbà ní Ìpínlẹ̀ Niger lọ́dún 2013 sí 2016.
Hon Fatima Lami Abubakar | |
---|---|
Adájọ́ àgbà fún Ìpínlẹ̀ Niger | |
In office March 2013 – April 2016 | |
Asíwájú | Hon. Justice Jibrin Ndajiwo |
Obìnrin àkọ́kọ́ fún Nàìjíríà àti Aya Ààrẹ-àná lọ́dún 1998 sí 1999 | |
In office June 1998 – May 1999 | |
Ààrẹ | Abdulsalami Abubakar |
Asíwájú | Maryam Abacha |
Arọ́pò | Stella Obasanjo |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Fatima Lami 12 Oṣù Kẹrin 1951 Minna, Nigeria |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Abdulsalami Abubakar |
Àwọn ọmọ | Six |
Wọ́n bí Fati lọ́jọ́ Kejìlá oṣù kẹrin ọdún 1951 ní ìlú Minna, ní [[Ìpínlẹ̀ Niger] [lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.Ó kàwé ni Queen Elizabeth School ní [[Ilorin], ní Ìpínlẹ̀ Kwara. Bẹ́ẹ̀ náà, ó kàwé ní Federal Government College, ní Ìpínlẹ̀ Sokoto, àti ní Obafemi Awolowo University, Ilé Ifẹ̀, ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Ó kàwé gboyè nínú ìmọ̀ òfin, bẹ́ẹ̀ náà ló kàwé gboyè ọ̀mọ̀wẹ́ nínú ìmọ̀ Philosophy. Bákan náà, Fati kàwé gboyè ní 'Nigeria Law School'.
Fati Lami fẹ́ Àárẹ̀ àná, Abdulsalami Abubakar, wọn sìn bí ọmọ mẹ́fà fún ara wọn.
Abubakar ti fẹ́ Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà kan rí, Abdulsalami Abubakar, ẹni tí ó bí ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú.
This article uses material from the Wikipedia Yorùbá article Fati Lami Abubakar, which is released under the Creative Commons Attribution-ShareAlike 3.0 license ("CC BY-SA 3.0"); additional terms may apply (view authors). Gbogbo ohun inú ibí yìí wà lábẹ́ CC BY-SA 4.0 àyàfi tí a bá sọ pé kò rí bẹ̀ẹ̀. Images, videos and audio are available under their respective licenses.
®Wikipedia is a registered trademark of the Wiki Foundation, Inc. Wiki Yorùbá (DUHOCTRUNGQUOC.VN) is an independent company and has no affiliation with Wiki Foundation.