Muhammadu Buhari (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ ketàdínlógún, Oṣù Kejìlá Odún 1942) olóṣèlú tí ó jẹ́ Ààrẹ orílè-èdè Nàíjíríà láàrin ọdún 2015 sí ọdún 2023.
Ó lo ṣáà àkọ́kọ́ rẹ̀ láàrin odún 2015 sí 2019 àti kejì láàrin ọdún 2019 sí 2023. Buhari tí fìgbà kan jẹ́ ogágun Méjọ̀ Gẹ́nẹ́rà àti pé ó j̣e olórí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lati 31st Oṣù kejìlá odún 1983 sí Oṣù kẹjó odún 1985, léyìn tí ó fi kúùpù ológun gbàjọba.
His Excellency Muhammadu Buhari | |
---|---|
Ààrẹ ilẹ̀ Nàìjíríà 7k & 15k | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 29 Oṣù Kàrún 2015 | |
Vice President | Yemi Osinbajo |
Asíwájú | Goodluck Jonathan |
Chair of the Supreme Military Council | |
In office 31 Oṣù Kejìlá 1983 – 27 Oṣù Kẹjọ 1985 | |
Vice President | Tunde Idiagbon (Chief of Staff) |
Asíwájú | Shehu Shagari (President) |
Arọ́pò | Ibrahim Babangida (Chair of the Armed Forces Ruling Council) |
Ijoba Ijoba ti Awọn Ọkọ Ẹrọ | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 11 Kọkànlá Oṣù 2015 | |
Asíwájú | Diezani Allison-Madueke |
Gómínà ìpínlẹ̀ Bọ̀nú | |
In office 3 Oṣù Kejì 1976 – 15 Oṣù Kẹta 1976 | |
Asíwájú | Position established |
Arọ́pò | Mustapha Amin |
Governor of the Northeastern State | |
In office 1 Oṣù Kẹjọ 1975 – 3 Oṣù Kejì1976 | |
Asíwájú | Musa Usman |
Arọ́pò | Position abolished |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 17 Oṣù Kejìlá 1942 Daura, Northern Region, Nigeria (now Daura, Katsina State, Nigeria) |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Safinatu Yusuf (m. 1971; div. 1988) Aisha Halilu (m. 1989) |
Àwọn ọmọ | 10 |
Alma mater | Nigerian Military Training College Mons Officer Cadet School U.S. Army War College |
Website | Official website |
Military service | |
Nickname(s) | Baba go slow |
Allegiance | Nàìjíríà |
Branch/service | Adigun Nàìjíríà |
Years of service | 1961–1985 |
Rank | Major General |
*Yemi Osinbajo served as Acting President from 19 January 2017 – 13 March 2017 and 7 May 2017 – 21 August 2017 while Buhari received medical treatment. |
A bí Muhammadu Buhari sí ìdílé Fulani ní ọjọ 17 Kejìlá 1942, ní Daura, Ìpínlè Katsina, baba rẹ ni Hardo Adamu, ẹni tí ó jẹ́ olori Fulani, orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Zulaihat, ẹni tí ó Hausa. Òun ni ọmọ kẹtalelogun bàbá rẹ̀. Ìyá Buhari ni ó tọ dàgbà, bàbá rẹ̀ fi ayé sílè nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́rinrin.
Buhari dara pò mó Nigerian Military Training College (NMTC) ní ọdun 1962, ó jẹ́ omo odun kan dínlógún nígbà náà. Ní oṣù kejì ọdún 1964, a yí orúkọ ilé-ìwé ológun náà padà sí Nigerian Defence Academy (NDA).
Ní àárín 1962 sí 1963, Buhari kó nípa ìmò ogun ní Mons Officer Cadet School ní ìlú Aldershot, England. Ní oṣù kínní ọdún 1963, nígbà tí Buhari jẹ́ ọmọ ọdún ogún, a sọ́ di lieutenanti kejì.
This article uses material from the Wikipedia Yorùbá article Muhammadu Buhari, which is released under the Creative Commons Attribution-ShareAlike 3.0 license ("CC BY-SA 3.0"); additional terms may apply (view authors). Gbogbo ohun inú ibí yìí wà lábẹ́ CC BY-SA 4.0 àyàfi tí a bá sọ pé kò rí bẹ̀ẹ̀. Images, videos and audio are available under their respective licenses.
®Wikipedia is a registered trademark of the Wiki Foundation, Inc. Wiki Yorùbá (DUHOCTRUNGQUOC.VN) is an independent company and has no affiliation with Wiki Foundation.