Àwọn èsì àwárí fún
Ojúewé tó ún jẹ́ "Bíbélì" wà lórí Wikipedia Ẹ tún wo àwọn èsì ìwárí míràn tó jáde.
Bíbélì Mímọ́, tabi Bíbélì jẹ́ àkójọpọ̀ àwọn ìwé Ẹ̀sìn Ju àti Ẹ̀sìn Kristi. Bibeli Heberu tabi Bibeli Awon Ju da si apa meta: Torah, tabi "Ilana" ti a... |
Ìwé Gẹ́nẹ́sísì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Gẹ́nẹ́sísì ni iwe ninu Bíbélì Mímọ́.... |
Episteli Kìnní sí àwọn ará Tẹsalóníkà (ẹ̀ka Bíbélì) Episteli Kìnní sí àwọn ará Tẹsalóníkà jẹ́ ìwé Májẹ̀mú Titun nínú Bíbélì Mímọ́.... |
Ìwé Léfítíkù (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Léfítíkù jẹ́ ẹsẹ Bíbélì Mímọ́, níbi tí àkọsílẹ̀ oríṣiríṣi ìṣẹ̀lẹ̀ ti wáyé.... |
Ìwé Ẹkún Jeremíàh (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Ẹkún Jeremáyà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa ìtìjú, ìjìyà, àti ìdààmú Jerúsálẹ́mù àti àwọn ènìyàn rẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ará Bábílónì pa ìlú wọn run... |
Orin Sólómọ́nì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Orin Sólómọ́nì jẹ́ ẹsẹ Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa ọba ọlọ́rọ̀ jùlọ, tí Ọlọ́run tún dá lọ́lá ọ̀gbọ́n tó jùlọ nítorí ìdásí ọrẹ ẹbọ tí ó fi fún Ọlọ́run... |
Ìwé Psalmu (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Psalmu (psalmu) orin Dáfídì jẹ́ ìwé mímọ́ nínú bíbélìBíbélì mímọ́.... |
Ìwé Ẹ́stérì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Ẹ́sítérì jẹ́ ẹsẹ Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa Ẹ́sítérì, múdíá, bí ó ṣe rí àánú Ọlọ́run gbà, tó di aya ọba, tí ó sì tún kó àwọn Ísírẹ́lì yọ lọ́wọ́ Hámánì... |
Ìwé Dáníẹ́lì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Dáníẹ́lì jẹ́ ẹsẹ Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa Dáníẹ́lì àti àwọn ìdojúkọ rẹ̀ ní ilẹ̀ àjòjì Bábílónì lọ́pọ̀, bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú àkọsílẹ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ oríṣiríṣi... |
Ìwé Jeremíàh (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Jeremáyà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa ìwé náà gẹ́gẹ́ bí i ìránṣẹ́ sí àwọn Júù tó wà ní ìgbèkùn ẹyin odi ní Bábílónì, tí ó jẹ́ pé èyí wáyé nípa... |
Ìwé Nehemíàh (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Nehemáyà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa àkókò kan nínú ìtàn àwọn Júù, ìyẹn bí i ìránṣẹ́ Ọlọ́run Nehemáyà ṣe padà sí Jerúsálẹ́mù láti bẹ̀rẹ̀ àti... |
Ìwé Númérì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Númérì jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti àwọn ìlàkàkà àti ìrìnàjò wọn nínú aginjù, ìyẹn bí wọ́n ṣe kúrò ní ilẹ Sínáì, tí wọ́n... |
Ìwé àwọn Oníwàsù (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé àwọn Oníwàásù jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa ìdùnnú níní nínú àwọn tí a ò fi bẹ́ẹ̀ kà kún, bí i oúnjẹ jíjẹ àti mímú. Bẹ́ẹ̀ kí a má rí ìdùnnú nínú... |
Ìwé Dẹutẹ́rónómì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Deutẹ́rómómì jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa irúfẹ́ ìṣẹ̀dá Ọlọ́run bí Ó ṣe tóbi tó, àti àwọn èrè ẹ̀ṣẹ̀ fún ẹni tó bá lòdì sí àwọn òfin àti ìlànà... |
Ìwé Ẹ́srà (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Ẹ́sírà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa ìpadà ìránṣẹ́ Ọlọ́run, àti àwọn ọwọ́ Júù méjì kan láti Bábílónì padà sí Jerúsálẹ́mù, níbi tí wọ́n ti tún... |
Goliati (jé òmìrán kan tí Bíbélì sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ nínú ìwé Sámúẹ́lì, Bíbélì ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi òmìrán ara filistini kan tí Davidi ségun lójú ogun.... |
Ìwé Hóséà (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Hóṣéà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó ń ṣàfiwé ìfẹ́ Hóṣéà sí aya rẹ̀ tó dẹ́ṣẹ̀ àgbèrè, tí ó ṣì fẹ́ràn tó sì gbà tọwọ́-tẹsẹ̀ padà. Tí ó sì jẹ́ wí pé, ní tòótọ́... |
Ìwé Sámúẹ́lì (ẹ̀ka Bíbélì) Ìwé Sámúẹ́lì jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa Sámúẹ́lì, ìbí rẹ̀, bí ó ti ṣe dàgbà nínú ìjọ lábẹ́ wòlíì Ọlọ́run kan Élì, tí ó sì jẹ́ láti ìgbà èwe rẹ̀... |
Májẹ̀mú Titun (ẹ̀ka Bíbélì) Majẹmu titun ni ìpín kejì tí Bíbélì mímọ Kristẹni. Ó sọ nípa àwọn ẹ̀kọ́ àti ìgbẹ́ ayé Jesu,o tún sọ nípa ìgbé ayé àwọn Kristẹni. Májẹ̀mú titun jẹ́ àpapọ̀... |
ẹ̀kọ́ Jesu ti Nasareti gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe kọsílẹ̀ nínú Májẹ̀mú Tuntun ti Bíbélì. Ẹ̀sìn ìgbàgbọ́ ló fẹ́rẹ̀ tan kálẹ̀ jù ní gbogbo àgbáyé. Ní bíi nkàn an... |